BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Akọrin, Ifunanya Nwangene jáde láyé lẹ́yìn tí ejò ṣan ní Abuja
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ Àìkú ní ìròyìn ikú Ifananya bẹ̀rẹ̀ sí kàn lórí ayélujára látàrá ìròyìn pé ejò ló san ọmọbìnrin náà tó fi jáde láyé lọ́jọ́ Àbámẹ́ta.
Níbo ni ọ̀rọ̀ dé lórí àwọn aṣọ́gbó ọba márùn-ún táwọn agbébọn pa ní ìpínlẹ̀ Oyo?
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Oyo, DSP Olayinka Alayande sọ pe eeyan meje lo ti wa lahamọ ofin bayii lori ipaniyan ati ikọlu naa.
Ọwọ́ àjọ NDLEA tẹ oníṣòwò tó kó oògùn olóró sí ojú ara l'Ekoo
Onyekwere, ẹni ọdun mẹtadinlaadọta, ni ọwọ tẹ l'Ọjọbọ, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kin-in-ni ọdun 2026 lasiko to fẹ wọle si Naijiria lati Brazil.
'Àwọn tó fẹ́ gbe Imam níjà lásìkò ti Najeem fẹ́ la gbohùngbohùn mọ́-ọn lórí ló lù ú pa'
Awọn olujọsin ni a gbọ pe wọn dawọ jọ lu ọkunrin naa pa lasiko irun Fajr, lori ẹsun pe o da waasi Imam ru.
Kí ni orísun fífà orí ọmọ tuntun?
Ọpọ awuyewuye lo ti jẹyọ lori eyi boya o dara fun ọmọ ikoko tabi ko dara.
Kí lohun tí Kunle Afolayan sọ nípa Funke Akindele tó fa ariwo lórí ayélujára?
Ọrọ ti Kunle sọ yii lo ti bẹrẹ si i mu oriṣiisii awuyewuye wa, bẹẹ lawọn mi-in n sọ pe niṣe ni oṣere naa n fi awọn Funke Akindele, Toyin Aimakhu atawọn miran to n gbe fiimu lọ si sinima ṣe yeyẹ.
Wo nǹkan mẹ́ta tó le ṣokùnfà kí ẹ̀jẹ̀ máa wà nínú ìgbọ̀nsẹ̀ rẹ
Ìwádìí fi hàn pé onírúurú nǹkan ló le fa kí ẹ̀jẹ̀ wà nínú ìgbẹ́ tí wọ́n sì le le ju ara wọn lọ.
Ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn ló máa báwa yanjú ọ̀rọ̀ - Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP fọnmú
Ileẹjọ tun fofin de iṣejọba Tanimu Turaki ninu ẹgbẹ oṣelu PDP, to si ni ki wọn ye pe ara wọn ni awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP lorilẹede Naijiria.
Ooni Adeyeye Ogunwusi: Ọọ̀ni tí a bí ní agogo kan géérégé bí àsọtẹ́lẹ̀, táwọn òbí rẹ̀ kò sí fọwọ́ kàn-án lórí láti'gbà èwe
Baba to bi Ooni Ogunwusi, Ọba John Olurọpo Ogunwusi, ṣalaye pe ki wọn too bi Kabiyesi naa ni asọtẹlẹ ti jade pe okiki rẹ yoo kan kaakiri agbaye.
Kwara: Ológun Naijiria yabo ibùba àwọn agbésùnmọ̀mí, gba àwọn tó wà nígbèkùn kalẹ̀
Ana ode yii ti i ṣe ọjọ Ẹti, ọgbọnjọ oṣu Kin-in-ni ọdun 2026 ni ileeṣẹ ologun Naijiria fi eyi lede loju opo X wọn.
Móríwú
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Ìdí rèé tí a kò fi ní tẹ́wọ́ gba èsì ìdìbò tí INEC bá kéde - SCSN
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC, abẹnugan ile, Sheikh Bashir Aliyu Umar, ṣalaye iha to kọ si alaga ajọ eleto idibo, to si tun kilọ pe awọn musulumi lorilẹede Naijiria ko ni tẹwọgba esi idibo kankan labẹ iṣakoso Amupitan.
Ohun méje tó ṣeéṣe kó wáyé tí Amẹrika bá ju àdó olóró sí Iran
Akọroyin BBC, Frank Gardner wo ohun to le ṣẹlẹ ti Amẹrika ba kọju ija si Iran lasiko yii.
Taa ni Stanley Amandi, òṣèré tíátà tí ìjọba mú lórí ẹ̀sùn pé ó wà lára àwọn tó fẹ́ dìtẹ̀gbàjọba lọ́wọ́ Tinubu?
Ẹnikan to sunmọ afurasi naa amọ ti ko fẹ ki a darukọ oun ni lootọ ni wọn fi ṣikun ofin gbe niluu Enugu.
Ìjọba ṣe àfikún ọjọ́ tí ìforúkọsílẹ̀ fún ètò ẹ̀yáwó àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò parí, wo bí o ṣe lè jànfààní rẹ̀
Ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu Kinni yii lo yẹ ki iforukọsilẹ naa pari tẹlẹ, ṣugbọn ajọ NELFUND ti sun ọjọ naa si ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu Keji to n bọ bayii.
Mi ò lè gbà kí ìyà jẹ ọkọ mi rara, ìdí nìyí tí mo fi ń wà lẹ́yìn rẹ̀ nígbà gbogbo - Oluremi Tinubu, ìyàwó ààrẹ Nàìjíríà
Aya Aarẹ Oluremi Tinubu sọ pe ''mi o lero pe mo le di aya aarẹ orilẹ-ede Naijiria rara.''
NAFDAC ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi fòfin de pẹlẹbẹ, fònàgáú àtàwọn ọ̀tí inú ọ̀rá míràn ní Naijiria
NAFDAC ni awọn ko sọ pe ki awọn olupese ọti ma gbe ọti sita ṣugbọn opin ti de ba ọti inu ọra lorilẹede Naijiria.
Anthony Joshua sọ̀rọ̀ lórí ìjàmbá ọkọ̀ tó gbẹ̀mí ọ̀rẹ̀ rẹ̀ méjì, Ó ní 'Ọkàn mi gbọgbẹ́'
Joshua ni ijamba ọhun ṣẹlẹ lojiji lẹyin toun atawọn ọrẹ oun mejeeji ti pinnu nnkan tawọn jọ fẹ ṣe papọ ni ipari ọdun to kọja.
Ohun tí a mọ̀ nípa ìbúgbàmù àti ìró ìbọn tó dún ní pápákọ̀ òfúrufú Niger
Awọn oṣojumikoro atawọn fidio lati ibẹ ṣafihan bi awọn ohun ija to n koju ado oloro lati oju ofurufu ṣe n siṣẹ.
CAF ní kí akọ́nimọ̀ọ́gbá Senegal san fáìnì N139m, kede faini N278m fún Morocco lórí awọn ọmọ tó fẹ́ jí aṣọ ìnujú Mendy
CAF ni Thiaw jẹbi ẹsun wi pe o tabuku ere bọọlu nigba to ni kawọn agbabọọlu Senegal kuro lori papa lẹyin ti rẹfiri fọn fere wi pe ki Morocco to jẹ alatako Senegal gba pẹnariti.
₦130b owó ìpínlẹ̀ Osun ni ìjọba àpapọ̀ dìmú láti ọdún kan sẹ́yin – Ademola Adeleke
Adeleke sọ pe owo naa ti ko tẹ ijọba ipinlẹ ọhun lọwọ n ṣakabo fun idagbasoke rẹ paapaa fun awọn eeyan to wa ni igberiko.
Mínísítà tẹ̀lẹ̀ fépo rọ̀bì ní Nàìjíríà farahan níléẹjọ́ fún ẹ̀sùn rìbá tówó rẹ̀ tó £2mílíọ̀nù ní Harrods
Diezani Alisson-Madueke ni minisita fun epo rọbi laarin ọdun 2011 si 2015.
Itan Manigbagbe: Oba Asanike Yefusu Oloyede, Olubadan tó gbóyà, aláwàdà, tó tún kún fún ọgbọ́n
Ọdun mẹwaa ni Asanikẹ lo lori oye Olubadan. Ọpọlọpọ si ni ko gbagbọ pe yoo lo to iye ọdun naa, nitori pe o ti di arugbo kujọ-kujọ ko to o jẹ ọba.
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ẹ fi Osugbo kún ìgbìmọ̀ afọbajẹ tí yóò yan Awujale tuntun- Ẹgbẹ́ Òsùgbó rọ Dapo Abiodun
Oluwo Osugbo niluu Ijebu-Ode, Omobolanle Bakare, fi aidunnu rẹ han si bi Osugbo ko ṣe si ninu igbimọ afọbajẹ ti yoo yan Awujalẹ.
Jide Kosoko di ọmọ oyè Oloja ìlú Eko
Jide Kosoko funra rẹ lo fidi iroyin naa mulẹ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwerọ kan
Ohun tí a mọ̀ rèé nípa àríyànjiyàn láàrin APC àti Gómìnà Adeleke tó ní sáà àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ APC l'Osun ti parí
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu APC naa da a pada fun gomina wi pe ko si ohun to jẹ bẹẹ rara.
"Ìtọ̀ ara mi ni mo mu fún ọjọ́ mẹ́jọ nínú igbó lẹ́yìn tí mo sá máwọn ajínigbé lọ́wọ́"
Arabinrin yii ti awọn araalu rẹ mọ si Iya Bẹskẹ ni awọn ajinigbe ji gbe papọ mọ awọn mẹwaa mii ni ilu Isapa losu kọkanla ọdun to kọja.
Iye ìgbà tí ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti wó ilé aráàlú láàárín ọdún kan sẹ́yìn
Iwọnyii lawọn agbegbe ti ijọba Eko ti wo ile laarin ọdun kan sẹyin.
Àṣírí ohun tó fa aáwọ̀ láàrín ẹbí Bunmi Akinnaanu 'Omije Oju mi' àtàwọn akọrin ẹ̀mí lórí ètò ìsìnkú rẹ̀ rèé
Igbagbọ ọpọ eeyan tẹlẹ ni pe awọn akẹgbẹ Omije Oju mi to ti kọkọ kede eto isinku rẹ, ṣugbọn ti ẹbi Oloogbe yi i pada yoo wa nibi eto ti mọlẹbi gbe kalẹ.
Ohun tí a mọ̀ nípa àbẹ̀wò Sunday Igboho sí Olubadan Ladoja, ohun tó sọ nípa yíyọ orúkọ rẹ̀ kúrò nínú àwọn tí ìjọba ń wá
Igboho sa kuro ni NAijiria lẹyin tawọn agbofinro ya bo ile rẹ lọdun 2021 lẹyin ti o lewaju gbigbogun ti awọn darandaran to n ṣọṣẹ lawọn agbegbe kan nilẹ Yoruba nigba naa.
Wo ohun tuntun tí iléeṣẹ́ ológun ń sọ nípa àwọn ọmọogun tó gbìyànjú gbígba ìjọba lọ́wọ́ ọ Tinubu, ohun tójú wọn yóò rí
Eyi wa ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ologun Naijiria fi soju opo ayelujara, pe ọmọ ologun mẹrindinlogun ni ọwọ tẹ ninu oṣu kẹwaa ọdun 2025, ti wọn ti si fi ẹsun ẹsun iwa ibajẹ ati titapa sofin kan wọn.
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Alex Pretti, arákùnrin táwọn agbófinró ICE pa ní Minneapolis, tí ikú rẹ̀ ń dá èdèàìyedè sílẹ̀ l'Amerika
Oṣiṣẹ eto ilera ni Alex nigba aye rẹ, o si fẹran ko maa jade, paapaajulọ lati maa wa kẹkẹ kaakiri awọn oke.
Agbésùnmọ̀mí kọlu Zamfara láago méjìlá òru, jí èèyàn 26 gbé lọ
Ibi ti iṣẹlẹ yii ti waye, Talatar Mafara jẹ ọkan lara awọn ijọba ibilẹ ti iṣẹlẹ ijinigbe ti maa n waye lemọlemọ lati ọdun 2021.











































































